Samuẹli Keji 17:24 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí Absalomu ati àwọn ọmọ Israẹli yóo fi ré odò Jọdani kọjá tán, Dafidi ti dé ìlú tí wọn ń pè ní Mahanaimu.

Samuẹli Keji 17

Samuẹli Keji 17:20-29