Orin Dafidi 4:6-8 BIBELI MIMỌ (BM)

6. Ọ̀pọ̀ eniyan ni ó ń bèèrè pé “Ta ni yóo ṣe wá ní oore?”OLUWA, tan ìmọ́lẹ̀ ojú rẹ sí wa lára.

7. Ìwọ ti fi ayọ̀ kún ọkàn miju ayọ̀ àwọn tí ó rí ọpọlọpọ ọkà ati ọtí waini nígbà ìkórè.

8. N óo dùbúlẹ̀, n óo sì sùn ní alaafia,nítorí ìwọ OLUWA nìkan ni o mú mi wà láìléwu.

Orin Dafidi 4