Nọmba 10:7-9 BIBELI MIMỌ (BM)

7. Nígbà tí ẹ bá fẹ́ pe àwọn ọmọ Israẹli jọ ẹ óo máa fọn fèrè, ṣugbọn kò ní jẹ́ ti ìdágìrì.

8. Àwọn alufaa, ọmọ Aaroni ni yóo máa fọn fèrè náà.“Fèrè yìí yóo sì jẹ́ ìlànà fún ìrandíran yín.

9. Nígbà tí ẹ bá ń lọ bá àwọn ọ̀tá yín jà lójú ogun láti gba ara yín lọ́wọ́ àwọn tí ń ni yín lára, ẹ óo fọn fèrè ìdágìrì. OLUWA Ọlọrun yín yóo sì ranti yín, yóo sì gbà yín lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá yín.

Nọmba 10