Ìwé Òwe 2:7-10 BIBELI MIMỌ (BM)

7. Ó fún àwọn tí wọn dúró ṣinṣin ní ìjìnlẹ̀ ọgbọ́n,òun ni ààbò fún àwọn tí wọ́n ń rin ọ̀nà ẹ̀tọ́.

8. Ó ń tọ́ wọn sí ìdájọ́ òtítọ́,ó sì ń pa ọ̀nà àwọn ẹni mímọ́ rẹ̀ mọ́.

9. Nígbà náà ni ìtumọ̀ òdodo ati ẹ̀tọ́ yóo yé ọati àìṣe ojuṣaaju, ati gbogbo ọ̀nà rere.

10. Nítorí ọgbọ́n yóo wọnú ọkàn rẹ,ìmọ̀ yóo sì tu ẹ̀mí rẹ lára,

Ìwé Òwe 2