Sekaráyà 6:10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Mú nínú ìgbèkùn, nínú àwọn Hélídáì, tí Tóbíyà, àti ti Jédáyà, tí ó ti Bábílónì dé, kí ìwọ sì wá ní ọjọ́ kan náà, kí o sì wọ ilé Jósáyà ọmọ Séfánáyà lọ.

Sekaráyà 6

Sekaráyà 6:2-13