Sáàmù 95:9-11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

9. Nígbà ti àwọn baba yin dán mi wòti wọn wádìí mi,ti wọn sì ri iṣẹ́ mi

10. Fún ogójì ọdún ni èmi fi bínú sí ìran náà;mo wí pé, “Wọ́n jẹ́ ènìyàn tí ọkàn wọn sáko lọwọn kò sì mọ ọ̀nà mi”.

11. Nítorí náà ni mo kéde ìbúra nínú ìbínú mi“Wọn kì yóò wọ ibi ìsinmi mi.”

Sáàmù 95