Sáàmù 67:4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Kí orílẹ̀ èdè kí o yọ̀, kí o sì kọrin fún ayọ̀,nítorí ìwọ fi òdodo darí àwọn ènìyànìwọ si jọba àwọn orílẹ̀-èdè ní ayé.

Sáàmù 67

Sáàmù 67:1-7