Sáàmù 59:13 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Pa wọn run nínú ìbínú,run wọ́n di ìgbà tí wọ́n kò ní sí mọ́.Nígbà náà ní yóò di mímọ̀ dé òpin ayépé Ọlọ́run jọba lórí Jákọ́bù. Sela

Sáàmù 59

Sáàmù 59:6-17