Sáàmù 119:1-5 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Ìbùkún ni fún àwọn ẹni tí ọ̀nà wọn wà láìlẹ́sẹ̀,ẹni tí í rìn ní ìbámu pẹ̀lú òfin Olúwa,

2. Ìbùkún ni fún àwọn ẹni tí ń pa òfin Rẹ̀ mọ́tí wọn sì ń wá a pẹ̀lú gbogbo ọkàn wọn.

3. Wọn kò ṣe ohun tí kò dára;wọ́n rìn ní ọ̀nà Rẹ̀.

4. Ìwọ ti la ìlànà Rẹ̀ sílẹ̀kí a sì pa wọ́n mọ́ gidigidi.

5. Ọ̀nà mi ìbá dúró ṣinṣinláti máa pa òfin Rẹ̀ mọ́!

Sáàmù 119