Sáàmù 107:1-5 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó ṣeun;nítorí ìfẹ́ Rẹ̀ dúró láéláé.

2. Jẹ́ kí àwọn ẹni ìràpadà Olúwa kí ó wí bayí, àwọnẹni tí ó ràpadà kúrò lọ́wọ́ ọ̀tá,

3. Àwọn tí ó kó jọ láti ilẹ̀ wọ̀nnìláti ìlà òòrùn àti ìwọ̀ òòrùn,láti àríwá àti òkun wá.

4. Wọn ń rìn káàkiri ni ihà ni ibi tí ọ̀nà kò sí,wọn kòrí ọ̀nà lọ sí ìlú níbi tíwọn ó máa gbé

5. Ebi ń pa wọn, òùngbẹ gbẹ wọn,ó sì Rẹ̀ ọkàn wọn nínú wọn.

Sáàmù 107