Róòmù 2:16 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Èyí yóò farahàn ní ọjọ́ náà nígbà tí Ọlọ́run yóò tipasẹ̀ Jésù Kírísítì ṣe ìdájọ́ àwọn àṣírí ènìyàn gẹ́gẹ́ bí ìyìn rere mi.

Róòmù 2

Róòmù 2:11-25