Róòmù 11:7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Kí ha ni? Ohun tí Isírẹ́lì ń wá kiri, òun náà ni kò rí; ṣùgbọ́n àwọn ẹni ìyànfẹ́ ti rí i, a sì ṣé àyà àwọn ìyókù le.

Róòmù 11

Róòmù 11:1-15