Róòmù 1:28 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Àti gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti kọ̀ láti gba Ọlọ́run nínú ìmọ̀ tí ó tọ́, Ọlọ́run fi wọ́n fún iyè ríra láti ṣe ohun tí kò tọ́ fún wọn láti ṣe:

Róòmù 1

Róòmù 1:19-32