Oníwàásù 11:9-10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

9. Jẹ́ kí inú rẹ dùn, ìwọ ọ̀dọ́mọdé ní ìgbà tí o wà ní èwekí o sì jẹ́ kí ọkàn rẹ fún ọ ní ayọ̀ ní ìgbà èwe rẹ.Tẹ̀lé ọ̀nà ọkàn rẹàti ohunkóhun tí ojú rẹ ríṣùgbọ́n mọ̀ dájú pé nípa gbogbo nǹkan wọ̀nyí niỌlọ́run yóò mú ọ wá sí ìdájọ́.

10. Nítorí náà, mú ìjayà kúrò ní ọkàn rẹkí o sì lé ìbànújẹ́ ara rẹ kúrònítorí èwe àti kékeré kò ní ìtumọ̀.

Oníwàásù 11