Onídájọ́ 9:35 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Gáálì ọmọ Ébédì jáde síta, ó sì dúró ní ẹnu ọ̀nà ibodè ìlú náà ní àkókò tí Ábímélékì àti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jáde kúrò níbi tí wọn sá pamọ́ sí.

Onídájọ́ 9

Onídájọ́ 9:26-37