Onídájọ́ 8:14 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ó mú ọ̀dọ́mọkùnrin kan ará Ṣúkótì, ó sì béèrè àwọn ìbéèrè ní ọwọ́ rẹ̀, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì kọ orúkọ àwọn ìjòyè Ṣúkótì mẹ́tadínlọ́gọ́rin (77) fún un tí wọ́n jẹ́ àgbààgbà ìlú náà.

Onídájọ́ 8

Onídájọ́ 8:7-23