Onídájọ́ 20:43 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Wọ́n yí àwọn ẹ̀yà Bẹ́ńjámínì ká, wọ́n lépa wọn, wọ́n sì pa wọ́n run pẹ̀lú ìrọ̀rùn ní ibi ìsinmi wọn ní agbégbé ìlà oòrùn Gíbíà.

Onídájọ́ 20

Onídájọ́ 20:42-45