Onídájọ́ 2:4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Bí ańgẹ́lì Olúwa sì ti sọ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn ará Ísírẹ́lì tan, àwọn ènìyàn náà sì gbé ohùn wọn sókè wọ́n sì sunkún kíkorò,

Onídájọ́ 2

Onídájọ́ 2:1-14