Nọ́ḿbà 31:30 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Lára ààbọ̀ ti Ísírẹ́lì, yan ọ̀kan kúrò nínú àádọ́ta, (50) yálà ènìyàn, ẹran ọ̀sìn, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àgùntàn, ewúrẹ́ tàbí ẹ̀yà ẹranko mìíràn. Kó wọn fún àwọn Léfì, tí ó dúró fún olùtọ́jú àgọ́ Olúwa.”

Nọ́ḿbà 31

Nọ́ḿbà 31:26-37