Nọ́ḿbà 22:8 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Ẹ sùn níbí lálẹ́ yìí” Bálámù sọ fún un pé, “Èmi ó padà wá fún un yín ní èsì nǹkan tí Olúwa bá wí fún mi.” Nítorí tí àwọn ìjòyè Móábù dúró sọ́dọ̀ rẹ̀.

Nọ́ḿbà 22

Nọ́ḿbà 22:7-18