Nọ́ḿbà 16:10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ó ti mú àwọn ènìyàn yín tó jẹ́ ọmọ Léfì súnmọ́ ara rẹ̀, ṣùgbọ́n báyìí ẹ tún ń wá ọnà láti ṣiṣẹ́ àlùfáà.

Nọ́ḿbà 16

Nọ́ḿbà 16:8-13