Nọ́ḿbà 12:15 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Míríámù sì dúró sí ẹ̀yìn ibùdó fún ọjọ́ méje, àwọn ènìyàn kò sì tẹ̀ ṣíwájú nínú ìrìnàjò wọn títí tí Míríámù fi wọ inú ibùdó padà.

Nọ́ḿbà 12

Nọ́ḿbà 12:14-16