Nehemáyà 6:7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

àti pé ó ti yan àwọn wòlíì kí wọn lè kéde nípa rẹ̀ ní Jérúsálẹ́mù: ‘ọba kan wà ní Júdà!’ Nísinsìn yìí, ìròyìn yìí yóò padà sí ọ̀dọ̀ ọba; nítorí náà wá, jẹ́ kí a bá ara wa sọ̀rọ̀.”

Nehemáyà 6

Nehemáyà 6:1-13