Nehemáyà 10:2-18 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

2. Ṣeráyà, Aṣaráyà, Jeremáyà,

3. Páṣùn, Ámáráyà, malikíjà,

4. Hátúsì, Ṣebanáyà, málúkì,

5. Hárímù, Meremótì, Obadáyà,

6. Dáníẹ́lì, Gínétónì, Bárúkì,

7. Mésúlámù, Ábíjà, Míjámínì,

8. Mááṣáyà, Bílígáì àti Ṣémáyà.Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà.

9. Àwọn ọmọ Léfì:Jéṣúà ọmọ Aṣanáyà, Bínúyì ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Hénédédì, Kádímélì,

10. àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn: Ṣébánáyà,Hódáyà, Kélítà, Péláyà, Hánánì,

11. Míkà, Réhébù, Hásábáyà,

12. Ṣákúrì, Ṣérébáyà, Ṣébánáyà,

13. Hódáyà, Bánì áti Benínù.

14. Àwọn olórí àwọn ènìyàn:Párósì, Páhátí-Móábù, Élámù, Ṣátù, Bánì,

15. Búnì, Áṣígádì, Bébáyì.

16. Àdóníjà, Bígífáyì, Ádínì,

17. Átérì, Heṣekáyà, Áṣúrì,

18. Hódáyà, Háṣámù, Béṣáyì,

Nehemáyà 10