Náhúmù 3:17 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Àwọn aládé rẹ̀ dàbí eṣú,àwọn ọ̀gágun rẹ dàbí ẹlẹ́ǹgà ńlá,èyí ti ń dó sínú ọgbà la ọjọ́ òtútù,ṣùgbọ́n nígbà tí òòrùn jáde, wọ́n sá lọẹnìkan kò sì mọ ibi tí wọ́n gbé wà.

Náhúmù 3

Náhúmù 3:8-19