Mátíù 8:20 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Jésù dá lóhùn pé, “Àwọn kọ̀lọ̀lọ̀kọ̀ ní ihò, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ni ìtẹ́; ṣùgbọ́n Ọmọ Ènìyàn kò ní ibi tí yóò fi orí rẹ̀ lé.”

Mátíù 8

Mátíù 8:11-24