Máàkù 6:50 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

nítorí gbogbo wọn ni ó rí i, tí ẹ̀rù sì bà wọ́n.Ṣùgbọ́n òun sọ̀rọ̀ sí wọn lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ pé, “Ẹ mú ọkàn le! Emi ni. Ẹ má bẹ̀rù.”

Máàkù 6

Máàkù 6:41-55