Lúùkù 12:46 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Olúwa ọmọ ọ̀dọ̀ náà yóò dé ní ọjọ́ tí kò retí rẹ̀, àti ní wákàtí tí kò dábàá, yóò sì jẹ ẹ́ níyà gidigidi, yóò sì yan ipò rẹ̀ pẹ̀lú àwọn aláìgbàgbọ́.

Lúùkù 12

Lúùkù 12:40-49