Léfítíkù 25:55 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Torí pé ìránṣẹ́ ni àwọn ọmọ Ísírẹ́lì jẹ́ fún mi. Ìránṣẹ́ mi ni wọ́n, tí mo mú jáde láti Éjíbítì wá. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

Léfítíkù 25

Léfítíkù 25:52-55