Léfítíkù 23:43 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Kí àwọn ìran yín le mọ̀ pé mo mú kí Ísírẹ́lì gbé nínú àgọ́, nígbà tí mo mú wọn jáde ní Éjíbítì. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ ”

Léfítíkù 23

Léfítíkù 23:39-44