Jóṣúà 4:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

kí ó sì jẹ́ àmì láàrin yín. Ní ọjọ́ iwájú, nígbà tí àwọn ọmọ yín bá béèrè lọ́wọ́ ọ yín pé, ‘Kí ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?’

Jóṣúà 4

Jóṣúà 4:3-16