Jóṣúà 22:26 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Nítorí èyí ni àwa ṣe wí pé, ‘Ẹ jẹ́ kí àwa múra láti mọ pẹpẹ kan, Ṣùgbọ́n kì í ṣe fún ọrẹ sísun, tàbí fún àwọn ìrúbọ.’

Jóṣúà 22

Jóṣúà 22:20-30