Jóṣúà 11:19 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Kò sí ìlú kan tí ó bá àwọn ará Ísírẹ́lì ṣe àdéhùn àlàáfíà, àyàfi àwọn ará Hífì tí wọ́n ń gbé ní Gíbíónì, gbogbo wọn ló bá a jagun.

Jóṣúà 11

Jóṣúà 11:11-23