14. “Ẹni tí àyà rẹ̀ yọ́ dànù, ta ni a bá máa ṣàánú fún láti ọ̀dọ̀ ọ̀rẹ́ rẹ̀ wá,kí ó má ba à kọ ìbẹ̀rù Olódumáarè sílẹ̀?
15. Àwọn ará mi ṣọ̀tẹ̀ bí odò sólobí ìṣàn gúru omi odò sólo, wọ́n ṣàn kọjá lọ.
16. Tí ó dúdú nítorí omi dídì,àti níbi tí odò dídì gbé lùmọ̀ sí.
17. Nígbà kúgbà tí wọ́n bá gbóná wọn a sì yọ́ ṣànlọ,nígbà tí òòrùn bá mú, wọn a sì gbẹ kúrò ni ipò wọn.