Jóòbù 39:1-4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. “Ìwọ mọ àkókò ìgbà tíàwọn ewúrẹ́ orí àpáta ìbímọ? Ìwọsì lè kíyèsí ìgbà tí abo àgbọ̀nrín ń bímọ?

2. Ìwọ lè ka iye òṣùpá tí wọn ń pè,ìwọ sì mọ àkókò ìgbà tí wọn ń bímọ,

3. Wọ́n tẹ ara wọn ba, wọ́n bí mọ,wọ́n sì mú ìkáànú wọn jáde.

4. Àwọn ọmọ wọn rí dáradára, wọ́ndàgbà nínú ọ̀dàn; wọ́n jáde lọ, wọn kò sì tún padà wá sọ́dọ̀ wọn.

Jóòbù 39