Jóòbù 37:20-24 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

20. A ó ha wí fún un pé, èmi fẹ́sọ̀rọ̀? Tàbí ẹnìkan lèwí pé, ìfẹ́ mi ni pé kí a gbémi mù?

21. Ṣibẹ̀ nísinsin yìí ènìyàn kò ríoòrùn tí ń dán nínú àwọ̀sánmọ̀,ṣùgbọ́n afẹ́fẹ́ ń kọjá, a sì fẹ́ wọn mọ́.

22. Góòlù dídán ti inú ìhà àríwá jádewá; lọ́dọ̀ Ọlọ́run ni ọláńlá ẹ̀rùn ńlá.

23. Nipa ti Olódùmarè àwa kò le wádìí rẹ̀; ó ré kọjá ní ipá; nínúìdájọ́ àtí títí bi oun kì í ba ẹ̀tọ́ àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ òtítọ́ jẹ́.

24. Nítorí náà ènìyàn ha máa bẹ̀rùrẹ̀; òun kì í se ojú sájú ẹnikẹ́ni tí ó gbọ́n ní ayé?”

Jóòbù 37