Jóòbù 27:21-23 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

21. Ẹ̀fúùfù ìlà oòrùn gbé e lọ, òun sìlọ; àti bí ìjì ńlá ó sì fà á kúrò ní ipò rẹ̀.

22. Nítorí pé Olódùmárè yóò kọ lù ú,kì yóò sì dá a sí; òun ìbá yọ̀ láti sá kúrò ní ọwọ́ rẹ̀.

23. Àwọn ènìyàn yóò sì ṣápẹ́ sí ilórí, wọn yóò sì ṣe síọ̀ sí i kúrò ní ipò rẹ̀.

Jóòbù 27