Jóòbù 23:10-13 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

10. Ṣùgbọ́n òun mọ ọ̀nà tí èmi ń tọ̀,nígbà tí ó bá dán mí wò, èmi yóò jáde bí wúrà.

11. Ẹṣẹ̀ mí ti tẹ̀lé ipaṣẹ̀ ìrìn rẹ̀; ọ̀nàrẹ̀ ni mo ti kíyèsí, tí ń kò sì yà kúrò.

12. Bẹ́ẹ̀ ni èmi kò padà sẹ́yìn kúrònínú òfin ẹ̀nu rẹ̀, èmi sì pa ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ mọ́ ju oúnjẹ òòjọ́ lọ

13. “Ṣùgbọ́n onínú kan ni òun, ta niyóò sì yí i padà? Èyí tí ọkàn rẹ̀ sì ti fẹ́, èyí náà ní í ṣe.

Jóòbù 23