Jòhánù 9:27 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ó dá wọn lóhùn wí pé, “Èmi ti sọ fún yín tẹ́lẹ̀, ẹ̀yin kò sì gbọ́: nítorí kínni, ẹ̀yin ṣe ń fẹ́ tún gbọ́? Ẹ̀yin pẹ̀lú ń fẹ́ ṣe ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bí?”

Jòhánù 9

Jòhánù 9:23-32