Jeremáyà 9:22 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Sọ pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí:“ ‘Òkú àwọn ènìyàn yóò ṣubúbí ààtàn ní oko gbangbaàti bí ìbùkúnwọ́ lẹ́yìn olùkórèláìsí ẹnìkankan láti kó wọn jọ.’ ”

Jeremáyà 9

Jeremáyà 9:15-25