Jeremáyà 51:55 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nítorí pé Olúwa ti ṣe Bábílónì ní ìjẹ,ó sì ti pa ohun ńlá run kúrò nínú rẹ̀;rírú wọn sì ń hó bi púpọ̀, a gbọ́ ariwo ohùn wọn.

Jeremáyà 51

Jeremáyà 51:51-63