Jeremáyà 51:39 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣùgbọ́n nígbà tí ọkàn wọn bá ru sókè,èmi yóò se àsè fún wọn,èmi yóò jẹ́ kí wọn mutí yó débití wọn yóò máa kọ ẹ̀rín lẹ́yìn náà,wọn yóò sun oorun àsùnjí,”ni Olúwa wí.

Jeremáyà 51

Jeremáyà 51:29-41