Jeremáyà 49:7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nípa Édómù:Èyí ní ohun tí Olúwa àwọn ọmọ ogun wí:“Ṣe kò ha sí ọgbọ́n mọ́ ni Temánì?Ṣé a ti ké ìmọ̀ràn kúrò ní ọ̀dọ̀ olóyè?Ṣé ọgbọ́n wọn ti bàjẹ́ bí?

Jeremáyà 49

Jeremáyà 49:3-14