Jeremáyà 31:27 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Wò ó, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “nígbà tí èmi yóò gbin ilé Ísírẹ́lì àti ilé Júdà pẹ̀lú irúgbìn ọmọ ènìyàn àti ẹranko.

Jeremáyà 31

Jeremáyà 31:23-29