Jeremáyà 29:26 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

‘Olúwa ti yàn ọ́ gẹ́gẹ́ bí àlùfáà rọ́pò Jéhóíádà láti máa jẹ́ alákóso ilé Olúwa, kí o máa fi èyíkéyìí nínú àwọn aṣiwèrè tó bá ṣe bí i wòlíì si inú àgò irin.

Jeremáyà 29

Jeremáyà 29:23-32