Jeremáyà 25:31 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ìrọ́kẹ̀kẹ̀ yóò wà títí dé òpin ilẹ̀ ayé,nítorí pé Olúwa yóò mú ìjà wá sí oríàwọn orílẹ̀ èdè náà,yóò mú ìdájọ́ wá sórí gbogbo ènìyàn,yóò sì fi àwọn olùṣe búburú fún idà,’ ”ni Olúwa wí.

Jeremáyà 25

Jeremáyà 25:22-34