Jeremáyà 2:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Orílẹ̀ èdè kan há á pa Ọlọ́run rẹ̀ dà?(Síbẹ̀, wọn kì í ṣe iṣẹ́ Ọlọ́run)àwọn ènìyàn mi ti pààrọ̀ògo wọn fún àwọn ère tí kò níyì.

Jeremáyà 2

Jeremáyà 2:2-15