Jẹ́nẹ́sísì 33:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Jọ̀wọ́ gba àwọn ohun tí mo mú wá wọ̀nyí lọ́wọ́ mi. Nítorí Ọlọ́run ti fi oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ hàn sí mi, gbogbo ohun tí mo fẹ́ sì ni mo ní.” Nígbà tí Jákọ́bù sì rọ̀ ọ́ pé Ísọ̀ gbọdọ̀ gbà wọ́n, Ísọ̀ sì gbà á.

Jẹ́nẹ́sísì 33

Jẹ́nẹ́sísì 33:8-20