Jẹ́nẹ́sísì 23:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

pé, “Rárá, Olúwa mi, Gbọ́ tèmi; mo fún ọ ní ilẹ̀ náà àti ihò àpáta tí ó wà níbẹ̀. Mo fún ọ níwájú gbogbo àwọn ènìyàn mi. Sin òkú rẹ ṣíbẹ̀.”

Jẹ́nẹ́sísì 23

Jẹ́nẹ́sísì 23:7-17