Jẹ́nẹ́sísì 17:5 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

A kì yóò pe orúkọ rẹ̀ ní Ábúrámù mọ́, bí kò ṣe Ábúráhámù, nítorí, mo ti sọ ọ́ di baba orílẹ̀ èdè púpọ̀.

Jẹ́nẹ́sísì 17

Jẹ́nẹ́sísì 17:1-11